Orísun: OJB News Yoruba | Akọroyin: Olalekan Akanji Ademeto, Abuja | Olootu: Lekan Lawal | Ojú-òpó: OJB Media Hub | Ọjọ Iṣẹgun, 1, Oṣù Kẹ̀sán 2026 | ojbmediashub.com.ng | +2348066952410
Ọkùnrin ẹni ọdún Mokanlelaadota (51) kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Hon. Brutus Egagha, tí wọ́n mọ̀ sí ‘Honorable’ tàbí ‘Ibroo-broo’, ni wọ́n rí òkú rẹ nínú duplex rẹ̀ ní Unity Close, Federal Housing Estate, Woji, nitosi Elelenwo, Port Harcourt, Rivers State.
ÌRÒYÌN ÌṢÁÁJÚ:
Ibo ọdún 2027, ọrọ b’ẹyin yọ bí àwọn òṣèlú alátakò ṣe lu’lẹ̀ níbi ìpàdé wọn nilu Abújá…
Eyii ni ìdí pàtàkì tí orilẹ-ede Amẹ́ríkà kò fi lè mú Ààrẹ Bọla Ahmed Tinubu fún ẹsun egbògi oloro……
Gẹgẹ bí ìròyìn:
Ara rẹ̀ ti wù ú, awọn amoye sọ pe o le ti ku to ọsẹ meji sẹhin
Security/gateman rẹ ko mọ, o ro pe o rin irin ajo lọ si UK lọdọ iyawo rẹ ati ọmọ mẹrin rẹ tóbi.
Òórùn burúkú tó ń rún ni o fa ki alabojuto ile wo inu parlour alejo, to ri oku rẹ lori sofa
Ile naa ni wọn ti pa mọ bi bio-hazard fun ayẹwo iṣoogun
Àkíyèsí Pàtàkì fún OJB News Yoruba:
Lórí ayélujára, ọ̀pọ̀ ẹ̀sùn àbòsì àti oògùn ìbílẹ̀ ń tàn kálẹ̀ nípa ọkùnrin náà àti àwọn ọmọbìnrin kan. Kò sí ẹ̀rí ọlọ́pàá tàbí ìwé ìwòsàn tó fìdí ẹ̀sùn wọ̀nyí múlẹ̀. Ọlọ́pàá Rivers State ṣi ń ṣe ìwádìí, a sì gbọdọ̀ dúró de abajade autopsy àti alaye osise.
OJB News Yoruba kì yóò tan ẹ̀sùn àìjẹ́rìí kálẹ̀. A rọ awọn oluka lati yago fun itankale aworan oku naa fun ọwọ ati lati jẹ ki awọn alaṣẹ ṣe iṣẹ wọn.
